Articles

Featuring Kọ́lá Túbọ̀sún

Nípa Ìkán-jù-kàn àti Ìpọ̀sí Èdè Nínú Lítiíréṣọ̀ Ilẹ̀ Afíríkà

Ó ti pé tí a ti máa ń gbọ́ àríyànjiyàn nípa kíni irú èdè tí ó yẹ ká lò láti máa kọ lítíréṣọ̀ nílẹ̀ adúláwọ̀. Ṣùgbọ́n ṣè kò tíì pẹ́ ju bẹ́ẹ̀ lọ tí àwọn ọmọ ilẹ̀ adúláwọ̀ ti ń ṣe oríṣiríṣi iṣẹ́ ọnà nínú èdè wọn?

Read full article